Àgbà òṣèré, Taiwo Hassan Ogogo ni àìsàn jẹjẹrẹ, a ń wá dókítà òyìnbó tàbí tí ìbílẹ̀ to le wò ó sàn - Àwọn ọmọ rẹ̀ figbe ta

Ọmọ Ogogo lobinrin, Shakira Taiwo lo fi Ikede yii síta pẹ̀lú ẹkún ńlá nínú fídíò kan tó ṣe láti fi béèrè fún ìrànwọ́.

Read full coverage on TraceNews