Gbàjarè oo! Inú àpò àṣùwọ̀n owó orí ayélujára 'crypto' ni wọ́n n jí owó ìjọba ìbílẹ̀ pamọ́ sí báyìí – EFCC figbe ta

Alaga ajọ EFCC, Ola Olukoyede lo fidi aṣiri yii mulẹ lọjọ Aje, ọsẹ yii lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Abuja.

Read full coverage on TraceNews