Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé

BBC News Yorùbá kàn sí gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, Ademola Adeleke láti fèsì sáwọn ẹ̀sùn tí wọn fi kan àwọn ẹgbọn rẹ pé wọn ti já àkóso ìjọba gbà mọ́ ọ lọ́wọ́.

Read full coverage on TraceNews