BBC News Yorùbá kàn sí gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, Ademola Adeleke láti fèsì sáwọn ẹ̀sùn tí wọn fi kan àwọn ẹgbọn rẹ pé wọn ti já àkóso ìjọba gbà mọ́ ọ lọ́wọ́.