Àlàyé rèé lórí ipa táwọn ikọ̀ aláàbò kó lórí báwọn Àgùnbánirọ̀ mẹ́ẹ̀dógún, aráàlú mẹ́fa, tí wọn jí gbé ní Kogi, ṣe gba ìtúsílẹ̀ àti ohun tí ààrẹ Tinubu sọ

Kii ṣe awọn agunbanirọ yii nikan lawọn ajinigbe digun ko salọ, bi ko ṣe pe wọn tun ji awọn araalu gbe pẹlu wọn, eyi ti apapọ gbogbo wọn jẹ mọkanlelogun.

Read full coverage on TraceNews