Ṣé òótọ́ ni pé INEC ti mọ ẹni tí yóò jáwé olúborí kí ètò ìdìbò tó wáyé?

Eniola Oladapo, to ṣoju ajọ INEC sọ fun BBC Yoruba niluu Abuja pe irọ gbu ni gbogbo awọn ọrọ naa ati pe ahesọ ọrọ lasan ni.

Read full coverage on TraceNews