Àwọn kan fẹ́ kí n sọ ₦25 milíọ̀nù tí Ogogo tọ́jú sọ́wọ́ mi di owó Mọ́ṣáláṣí ṣùgbọ́n mo ní rárá – Ìmáàmù ìlú Ilaro

Imaamu Adewumi ni lẹyin abẹwo ti oun ṣe gbẹyin si Ogogo nigba to wa ni ileewosan to n gba itọju lo san owo naa si aṣuwọn oun.

Read full coverage on TraceNews