'Ẹ̀yin nìkan kọ́ ló ń kojú ìṣòro iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì' - Ààrẹ Adama Barrow sọ̀rọ̀ lórí ìwọ́de ìdákúrekú iná tó ń wáyé ní Gambia

Awọn eeyan lorilẹede Gambia n ṣe iwọde nitori idakureku ina ọba to n ṣẹlẹ lorilẹede naa lati oṣu kẹfa.

Read full coverage on TraceNews